(Translated by https://www.hiragana.jp/)
Lukman Shobowale - Wikipedia, ìwé-ìmọ̀ ọ̀fẹ́ Jump to content

Lukman Shobowale

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lukman Shobowale
Ọjọ́ìbíLukman Olawale Shobowale
29 Oṣù Kàrún 1994 (1994-05-29) (ọmọ ọdún 30)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iléẹ̀kọ́ gígaUniversity of Ilorin, Ajayi Crowther University, Lagos Business School
Iṣẹ́Olùgbéejáde ọhún-iní gídí atí Onkọ́wé
Gbajúmọ̀ fúnCEO/Co-founder Dukiya Investments
Olólùfẹ́Oluwapelumi Shobowale
Websitelukmanshobowale.com/

Lukman Olawale Shobowale (tí á bí ní Ọjọ́ kàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 1994) jẹ́ Onkọ́wé atí Onísòwò Nàìjíríà. Òún ní olùdásílẹ̀ atí Alàkóso Dukiya Investments.[1]

Lukman ní olùdásílẹ̀ tí Dukiya Investments Limited, ilé-iṣẹ́ ìdàgbàsókè ọhun-iní gídí kán tí ọ dà lórí Èkó.[2][3][4] Ọ jẹ́ onkọ́wé atí tún ṣé iranṣẹ́ bí olórí Ìdàgbàsókè Ìṣòwò ní Dukiya Investments LTD. Lukman jẹ́ olókìkí fún ọhun-iní gídí, ìṣòwò, kíkọ, atí adári.[5][6] Ọ ṣé agbéró fún lílò ọhun-iní gídí láti kọ́ ọ́rọ̀ fún àwọn ìran iwájú. Làkọkó iwé-ẹ̀kọ́ oyè rẹ ní History and International Studies ní Ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásítì ìlú Ilorin, ọ ṣíṣẹ́ bí Alàkóso Ẹgbẹ́ ọmọ ilé-ìwé fun6 ọdún ẹ̀kọ́ 2016/2017.[7] Lukman gba Aami-ẹ́ri Ìṣòwò 2023 ní ọdún 2023 nípaṣẹ The Future Awards Africa.[8]Lukman jẹ́ oluyọ́ọ́da tí ọ tún ṣé àwọn iṣẹ́ aláànu.[9][10]

Lukman jẹ́ ọmọ ilé-ẹ̀kọ́ tí Yunifásítì ìlú Ilorin, níbití ọ tí kọ́ ẹ̀kọ́ Ìtàn atí Ìjìnlẹ̀ Káríayé fún Bachelor of Art Degree ṣáájú kí ọ tọ lọ́ sí Ilé-ẹ̀kọ́ Ajayi Crowther University fún Masters ní Ìṣàkóso Ìṣòwò ní ọdún 2021.[11] Ọ tún lọ́ síwájú sí Ilé-ìwé Ìṣòwò tí Èkó fún Ẹtọ Àwọn Alàkóso Ọlọhun.[11][12] Ọ ní àwọn ẹtọ aláṣẹ ní Ilé-ìwé Ìṣòwò Rome ní ọdún 2023 atí Ilé-ìwé Ìṣòwò Ìlú Lọndọnu ní ọdún 2024.[13]

Àwọn ìwé ọhún

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  • The Real Value of Wealth: Thoughts on Real Estate, Nigeria, and the Global Economy August 6, 2023.[14]
  • EMERGE! Like A Lotus In The Pond.[15]

Ìgbésí ayé ará rẹ

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọ ní ìyàwó sí Oluwapelumi Shobowale pẹlú ọmọbìnrin kán.


Àwọn ìtọkásí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Rapheal (2023-05-31). "Lukman Shobowale, Paul Olajide among realtors going strong". The Sun Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  2. "Dukiya investments rebrand cooperate identity to deliver excellent service". BusinessDayNG (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Jan 31, 2022. Retrieved June 21, 2023. 
  3. housingcablemgr (2023-01-06). "YOUNG REAL ESTATE PLAYERS TO WATCH IN 2023 - Housing Cable Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  4. "Lukman Shobowale's Dukiya Investment rated among top 100 SMEs in Nigeria". The Lekki Post (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-01-29. Retrieved 2023-06-21. 
  5. "Antidote to Housing Deficit in Nigeria - THISDAYLIVE". www.thisdaylive.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  6. "Addressing the housing deficit in Nigeria". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-02-15. Retrieved 2023-06-21. 
  7. "University of Ilorin Student Union History". UnilorinSU.com (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved June 21, 2023. 
  8. Africa, Glamour South (October 21, 2023). "Meet the Future Awards Africa 2023 Nominees". Glamour SA (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved March 22, 2024. 
  9. Suleiman, Yemisi (January 7, 2024). "Bayo Lawal And Lukman Shobowale: Defining New Trends in Real Estate". Vanguard Allure (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved March 22, 2024. 
  10. Unilorin, Ucj (May 9, 2023). "Lagos Real Estate Chiefs Storm Unilorin for AESA Leadership and Entrepreneurship Summit – UCJ UNILORIN". UCJ UNILORIN (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved March 23, 2024. 
  11. 11.0 11.1 Nigeria, Guardian (December 11, 2022). "Dukiya co-founders complete executive programme at Lagos Business School". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved June 22, 2023. 
  12. housingcablemgr (2023-01-06). "YOUNG REAL ESTATE PLAYERS TO WATCH IN 2023 - Housing Cable Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  13. "Real Estate Entrepreneur Lukman Shobowale Completes Executive Programme at London Business School". THISDAYLIVE (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). March 23, 2024. Retrieved March 23, 2024. 
  14. Ibeh, Ifeanyi (2023-07-07). "Lukman Shobowale announces book on Nigeria's real estate and housing potential". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2023-08-04. Retrieved 2023-08-04. 
  15. Reporter (2017-09-27). "The book titled - Emerge! like a lotus in the pond by Lukman Shobowale.". City People Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-08-04. 
  16. "Real estate solidified my interest in entrepreneurship, people – Lukman Shobowale". Tribune Online NG (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). November 1, 2023. Retrieved November 2, 2023. 
  17. "Lukman Shobowale bags RECRA's 2023 'Entrepreneur Of The Year'". Leadership.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2023-05-21. Retrieved June 21, 2023. 
  18. Rasak, Adekunle (2020-01-17). "Shobowale clinches Ooni's '100 Nigerian youth leaders' award". Tribune Online (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  19. housingcablemgr (2023-01-06). "YOUNG REAL ESTATE PLAYERS TO WATCH IN 2023 - Housing Cable Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-21. 
  20. "Unilorin Bulletin 7th November, 2016". Issuu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). November 7, 2016. Retrieved June 22, 2023.